Business

N I G E R I A

Africa In Miniature

World News in Yoruba


From The BBC

Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Kola Oyewo, àgbà òṣèré tíátà Yoruba tó jáde láyé
Àwọn gbajúmọ̀ òṣèré bíi Kunle Afod ati Yomi Ọlọrunlaiye ni wọ́n ti ń daro ipapoda àgbà òṣèré náà.


Mo máa pèsè ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ fáráàlú tí mo bá di gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti – Segun Akande
Segun Akande lo sọ bẹẹ ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC Yoruba.


Iléeṣẹ́ ológun Naijiria kéde àwọn agbéṣùmọ̀mí méjì tó juwọ́ sílẹ̀ fún ìjọba
Ileeṣẹ Ologun to fi iroyin naa lede lori ayelujara kede orukọ awọn agbeṣumọmi ti wọn juwọ lẹ naa bii Ismail Mohammed ati Abu Umar.


Ìfẹ̀hónúhàn wáyé káàkiri àwọn ìpínlẹ̀ lórí ààbò tó mẹ́hẹ, bèèrè fífi òpin sí ìjínigbé
Latari bi nnkan ko ṣe fararọ kaakiri lorilẹede Naijiria bayii, paapaa lẹka aabo ati ọrọ aje, ọpọ araalu ni inu wọn ko dun.


Iru Ekun nawọ́ gán afurasí ajínigbé méjì, dóòlà èèyàn méjì tí wọ́n jí gbé ní Osun
Ni ọjọru ni ẹṣọ aabo naa ni awọn ṣe iṣẹ naa lẹyin ti awọn gba iroyin pe awọn afurasi ajinigbe ji eeyan mẹta kang be ni ilu naa, ti wọn si ko wọn wọgbo lọ.


Bí ilé aṣojú-ṣòfin ṣe fòńtẹ̀ lu àbá ìdásílẹ̀ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀, wo ìlànà ìṣẹ́ wọn, àǹfààní àti ewu rẹ̀
Lasiko ti wọn dibo lori aba naa lati gba a wọle, aṣofin 288 lo faramọ ọn, nigba ti awọn mẹrin sọ pe awọn ko fẹ idasilẹ ọlọpaa ipinlẹ.


Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
Kò ṣeé má gbọ̀ọ́


Kókó ọ̀rọ̀ méje tí Tinubu sọ láti sàmì àyájọ́ June 12 àti àwọn tó gba àmì ẹ̀yẹ fọ́dún kẹtàdínlọ́gbọ̀n ìjọba àwaarawa
Nigba to n ṣide ọrọ rẹ, Aarẹ Tinubu sọ pe bo tilẹ jẹ pe ijọba awaarawa asiko yii ko gun rege, sibẹ, oun lo pẹ ju, tẹni si ni tẹni.


Yàtọ̀ sí June 12, àlàyé rèé nípa àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ mẹ́fà míì tí kò bá ti sọ Nàíjíríà sójú ogun abẹ́lé
BBC News Yoruba fi wọ inu itan lọ lati se agbeyẹwo igba meje ọtọọtọ ti ẹpọn agbo Naijiria ti mi, amọ ti Ọlọrun ko jẹ ko ja.


Wo àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tó sọ ''June 12'' di àyájọ́ ìjọba tiwantiwa àti mánigbàgbé yíká Nàìjíríà títí di òní
Lónìí àyájọ́ June 12, BBC News Yorùbá wọ inú ìtàn lọ láti ṣàlàyé àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé tí June 12 ṣe di ọjọ́ ìjọba alágbádá àti mánigbàgbé nínú ìtàn Nàíjíríà.


'A gba ìjọba arawa, a fi ń nira wa lára' - Àwọn aráàlú sọ èrò wọn lórí ọdún mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n ìṣèjọba àwaarawa
Lati ọdun 1960, ti ilẹ Naijiria ti gba ominira, ilana iṣejọba alagbada ko fi bẹẹ pẹ to bi awọn ologun ti dari ko to di ọdun 1999 ti wọn gbe ijọba le alagbada lọwọ.


Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Kwara nawọ́ gán afurasí ajínigbé mẹ́sàn-án, àkàrà bá tú sépo
Atẹjade kan ti agbenusọ ileeṣẹ ọlọpaa Kwara Adetoun Ejire-Adeyemi fi lede ṣalaye pe yatọ si awọn afurasi ajinigbe naa, ọwọ ọlọpaa tun tẹ ọkunrin kan ti igbagbọ wa pe o n ṣe agbodegba fun awọn ajinigbe ni ijọba ibilẹ Batuten.


Àwọn agbábọ́ọ̀lù méje tí ilẹ̀ Africa ń fojú sọ́nà fún ní ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé 2026
BBC Sport Africa ṣe agbeyẹwo awọn agbabọọlu meje lati foju sọna fun nibi idije ife ẹyẹ agbaye to maa waye ni awọn orilẹ ede United States, Mexico ati Canada lati ọjọ Kọkanla, oṣu Kefa, ọdun 2026.


Ìtàgé tó jìn mọ́ Gómìnà Adeleke àtàwọn ikọ̀ rẹ̀ lẹ́sẹ̀ níbi ìpolongo ìbò l'Osun, ohun tí a mọ̀ rèé
Ilu Ijebu-Jesa, nijọba ibilẹ Oriade ni iṣẹlẹ naa ti waye.


Agbébọn pa èèyàn mẹ́ta nílé ẹ̀kọ́, ọlọ́pàá, ológun, fijilanté dènà ìjínigbé, pa agbébọn kan
Ọjọru, ọjọ kẹwaa oṣu Kẹfa ọdun 2026 yii ni awọn agbebọn to to ogoji niye, ya wọ ile ẹkọ naa pẹlu alupupu ti wọn gun wa.


Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ


Ìdí mẹ́rin tí nǹkan ọkùnrin ṣe máa ń nàró ní àárọ̀ tí wọn bá jí
Nínú Fídíò yìí, BBC News Yorùbá ṣe ìwádìí nípa ídí tí nǹkan ọkùnrin ṣe máa ń nàró ní àárọ̀ tí wọn bá jí àti ohun tó ń fà á.


Àwọn agbébọn ṣíná ìbọn bolẹ̀ nígboro South Africa, èèyàn méjìlá kú, mẹ́sàn-án farapa
Gẹgẹ bi akọsilẹ ṣe fi han, orilẹede South Africa wa lara awọn ilu ti wọn ti n pa eeyan ju lagbaaye.


Ẹgbẹ́ City Boys tó ń ṣàtìlẹyìn fún Tinubu l‘Oyo ṣàbẹ̀wó sí Esinele, gbé ohun èlò ìwòsàn kalẹ̀, àmọ́ ẹbí Tíṣà tí agbébọn pa kọ àpò ìrẹsì àti owó Ìyálọ́jà, tíí ṣe ọmọ ààrẹ
Nigba to n sọrọ lasiko abẹwo ọhun, Onireti fi ireti han pe wọn maa ṣawari awọn akẹkọọ atawọn olukọ tawọn ajinigbe naa ji gbe laipẹ, bi o ṣe ni pe ijọba n sapa wọn lati gba itusilẹ awọn eeyan naa.


DSS lọgun pé àgbébọn fẹ́ kọlu iléẹ̀kọ́ l‘Edo, ìjọba ti iléẹ̀kọ́ mẹ́ta pa
Iwe kan lo lu sita lori ayelujara lojiji, eyi ti ikọ alaabo DSS fi sin ileeṣẹ NSCDC ti a mọ si aabo ara ẹni ni aabo ilu ni gberẹ ipakọ, pe awọn afurasi n mura lati kọlu awọn ile ẹkọ l'Edo.


Janmole sọ fún mi kó tó kú nípa ohun tó fẹ́ ṣe pẹ̀lú àbíkẹ́hìn rẹ̀ láìmọ̀ pé ikú ti súnmọ́ - Alfa
BBC News Yorùbá wà níbi àdúrà ọjọ́ kẹjọ gbajúmọ̀ àgbà òṣèré tíátà, olóògbé Fatai Okiki Adeshina Oshin, ti ọpọ eeyan mọ si Janmọlẹ, ohun tí a mú bọ̀ rèé.


Ẹ̀sùn jìbìtì N69m mí-ìn tún wọlé tọ Blessing CEO, yàtọ̀ sí ti 36m tí wọ́n kọ́kọ́ torí rẹ̀ fi pamọ́ sí àhámọ́
Ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kẹsan-an oṣu Kẹfa ni ile ẹjọ giga ipinlẹ Eko fi aaye oniduuro silẹ fun Blessing to ti wa lahamọ EFCC lati oṣu to kọja, pẹlu miliọnu mẹwaa naira, ṣugbọn ahamọ EFCC lo pada si.


Kí ni òfin sọ nípa wíwo ilé táwọn ajínigbé bá fi ṣe ibùgbé?
BBC News Yoruba kan si amofin Ademola Owolabi lati ṣalaye ohun ti ofin sọ nipa wiwo ile tawọn ajinigbe ba n lo fi ṣe ibugbe.


MURIC, ẹgbẹ́ Mùsùlùmí nàká àìtọ́ síjọba Oyo pé ó ló ìjínigbé Ogbomoso tako Islam, ìjọba sọ ìdí tí kò ṣe ní fèsì sí ẹ̀sùn náà
Kọmiṣọna fun eto iroyin ni ipinlẹ Oyo, Ọmọba Dotun Oyelade, sọ fun BBC Yoruba wi pe lati ọjọ ti wọn ti ji awọn akẹkọọ ati olukọ lọ ni Esinele ati Yawota l’Ogbomoso ni ijọba ti pinnu pe oun ko ni maa ṣe arohunbọhun pẹlu ẹnikankan lori iṣẹlẹ naa.


Amẹ́ríkà àti Iran ń da àdó olóró bo ara wọn léraléra fún ọjọ́ méjì
Aarẹ Amẹrika, Donald Trump ti fẹsun kan Iran pe o yin ado oloro ba ọkọ ofurufu hẹlikọpita oun ni ẹgbẹ Strait of Hormuz, to si ṣe ikọlu si Iran pada lati gbẹsan.


Rélùwéè yà kúrò lójú irin, èèyàn mẹ́ta kú
Ileeṣẹ NRC to n ri si ọrọ ọkọ ofurufu ni Naijiria, ṣalaye pe ẹka mẹrin lo ya kuro lara ọkọ oju irin naa.


Èèyàn mẹ́rin míràn ni ajínigbé tún pa ní Mowe, kì í ṣe ṣọ́jà nìkan - Iléeṣẹ́ ológun
Ninu atẹjade ti Ọgagun Idereghi Samuel Akari, Igbakeji ọga to n ri si ikede nileeṣẹ ologun 35 Artillery Brigade, Alamala niluu Abeokuta, fi sita lo ti ṣalaye eyi.


Àṣírí abilékọ̀ tó jí ara rẹ̀ gbé, béèrè ₦50m owó ìtúsílẹ̀ tú, ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ̀ ẹ́ pẹ̀lú ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ nílé ìtura
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Edo, Eno Ikoedem, ni lọjọ kinni oṣu Kẹfa yii ni ọkunrin kan niluu Benin fi to ọlọpaa pe wọn ti ji iyawo oun, Oluchi Ugbowan ẹni ọdun marundinlaadọta gbe lọ.


Ikọ̀ ọmọ ogun Isreali ṣekúpa olórí Hamas, Abu Karim
Ọjọ Aiku, ọjọ keje oṣu Kẹfa ọdun 2026 ni ikọ ologun Israeli sọ eyi di mimọ loju opo X wọn ti wọn ti kede.


'Ẹ̀sìn àbáláyé ló le yọ Nàìjíríà kúrò nínú ìpèníjà ààbò'
Bi awọn araalu ṣe n wa ojutuu si ipenija aabo Naijiria ni awọn ori ade ọrun ilẹkẹ ko dakẹ, ti wọn n fi imọran lede lori ọna ti wọn ro pe o le mu aabo pada silu.


Ẹ lo agbára àwọn alálẹ̀ láti ṣẹ́gun ìgbéṣùmọ̀mí - Ooni
Ninu alaye rẹ, Ooni Ogunwusi sọ pe o di dandan fun awọn ọba alaye kaakiri ilẹ Yoruba lati mu agbara iṣẹdalẹ lo.


Ṣé lóòótọ́ ni pé Sunday Igboho ló ṣe bí wọ́n ṣe gba ìtúsílẹ̀ àbúrò Adelabu àtàwọn ọmọ rẹ̀? Ohun tí a mọ̀ rèé
Alẹ ọjọ Satide, ọjọ kẹfa oṣu Kẹfa ọdun 2026 yii ni ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria fidi eyi mulẹ, ninu atẹjade ti Alukoro apapọ; DCP Anthony Okon Placid, fi sita l'Abuja.


Mò sunkún lórí àwọn ọmọ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso, mi ò mọ̀ pé tèmi náà yóò ṣẹlẹ̀ sí mi - Iya Adelabu
‎Kọmisona ọlọpaa Oyo ṣàlàyé pe awọn oṣiṣẹ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ ti ijọba apapọ, pẹlu àjọṣepo awọn oṣiṣẹ ile iṣẹ ọlọ́pàá nipinlẹ Oyo lọ pawọpọ sisẹ idoola ẹ̀mí náà.


Ohun tí a mọ̀ rèé nípa ìdúnkokò àwọn agbébọn láti ṣèkọlú sí ilé ẹ̀kọ́ ní Eko
Lara awọn ibi ti wọn darukọ ninu awọn fidio naa pe awọn agbebọn ti balẹ si ni ipinlẹ Eko ni agbegbe Lekki ati Ikorodu ati pe awọn ọlọpaa ti nawọ gan awọn kan ninu awọn agbebọn naa.


Ìdí tí ilé ẹjọ́ fi ní ₦110bn tílé aṣòfin àpapọ̀ fi ra ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́, pín fún àjẹmọ́nú wọn, lòdì sófin
Adajọ Yellim Bogoro lo gbe idajọ kalẹ lori ẹjọ ti ajọ ajafẹtọọmọniyan, SERAP pe ẹjọ lori pe ko ba ofin mu bi awọn aṣofin ṣe na owo naa.


Kí ló mú kí Iyabo Obasanjo fi ẹgbẹ́ APC sílẹ̀ lẹ́yìn tó lulẹ̀ láti díje fún ipò gómìnà?
Tẹ o ba gbagbe, ni nnkan bii oṣu diẹ sẹyin ni Iyabo Obasanjo kede pe oun fẹ dupo gomina ipinlẹ Ogun, ninu ẹgbẹ oṣelu APC.


Ṣé Adunni Ade onítíátà bímọ fún ọkọ ọlọ́kọ ni, ló ṣe gbé oyún àtọmọ tó bí lọ́dún méjì sẹ́yìn pamọ́? Áláyé rèé
Adunni Ade ṣalaye pe aijẹ kaye mọ nipa oyun atọmọbinrin toun bi ki i ṣe ti pe wọn ko gbọdọ mọ.


Ṣé lóòótọ́ ni Boko Haram yọ̀ǹda èèyàn 416 tí wọ́n jí gbé ní Borno? Ohun tí a mọ̀ rèé
Ọpọ obinrin ati awọn ọmọde ni wọn pe awọn ti wọn ni Boko Haram tu silẹ naa.


Ìgbákejì alága ìjọba ìbílẹ̀ l'Ekiti tí ọlọ́pàá ló jí ara rẹ̀ gbé dèrò àtìmọ́lé
Ogunjọ osu karun ọdun 2026 niroyin kan jade wi pe wọn ti ji arabinrin Ogunleye, igbakeji alaga ijọba ibilẹ ilejemeje gbe lọ nipinlẹ Ekiti.


Èyí lohun tí òfin sọ nípa àwọn tó bá ń gbé ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ pé jàndùkú wọ ìlú àti ìjìyà tó wà fún un
Awọn ipinlẹ ti awọn eeyan ti gbe iroyin ẹlẹjẹ pe agbesunmọmi wọ ilu ati ohun ti ofin sọ nipa pinpin iroyin ẹlẹjẹ.


Ṣé lóòótọ́ ni ọmọbìnrin akẹ́kọ̀ọ́ kan ti kú sígbèkùn ajínigbé nínú àwọn tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso? Àlàyé rèé
Iroyin naa lo tubọ mu ibanujẹ ati ikayasoke wa, bẹẹ ni o da omi tutu si ọkan ọpọ ọmọ Naijiria.


Àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú jànkàn tó lè má kópa nínú ètò ìdìbò ọdún 2027
Eyii ko ṣẹyin awọn oniruru ipẹjọ to n waye lẹyin alakalẹ INEC naa.


Oriyomi Hamzat ṣàlàyé àjọsẹpọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú Sheikh Gumi, ìgbésùnmọ̀mí àti akatakítí ẹ̀sìn
Ni itẹsiwaju alaye rẹ, Oriyomi Hamzat sọ pe oun ko ṣalaye ọrọ yii nitori ki araalu le dibo foun rara.


Nàìjíríà kéde èròńgbà láti kó àwọn èèyàn rẹ̀ ní South Africa padà sílé bí ìwọ́de tako àwọn àjòjì ṣe tún peléke síi
Igbesẹ yii lo n waye bi iwọde tako awọn ajoji ṣe n peleke si ni South Africa, tawọn orilẹ ede si n kọminu lori awọn eeyan wọn to wa ni South Africa.


Yinka Alaseyori ṣàlàyé ara rẹ̀ lórí fídíò tó ṣe nípa àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àtàwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso
Ṣaaju ni Yinka ti sọ ninu fidio kan to gbe jade wi pe kawọn ọmọ Naijiria tẹsiwaju lati maa gbadura lori eto aabo to mẹhẹ.


Saheed Osupa, gbajúmọ̀ akọrin fuji ti pariwo síta lórí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso; ohun tó sọ rèé
Lọjọ kẹẹdogun oṣu Karun un to kọja lawọn janduku agbebọn yabo ile ẹkọ girama Esinele ati ile ẹkọ alakọbẹrẹ ijọ Onitẹbọmi Baptist Nursery and Primary School ni Yawota nibi ti wọn ti ji eeyan to le logoji gbe.


INEC àti DSS bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lẹ́yìn tí àlàyé nípa olùdìbò lu síta lórí ayélujára
Ninu atẹjade kan lọjọ Iṣẹgun, INEC sọ pe oun gbe igbesẹ yii lẹyin ti iroyin nipa oloṣelu kan to tun jẹ gbajugbaja oṣere tiata, Emeke Ike, lu sita loju opo Continuous Voter Registration (CVR) ajọ naa.


One Step At A Time

This old adage, more relevant than ever



Our Objective

  • Support and encourage current members as and when the need arises fairly and honestly
  • Grow our membership by reaching out through formal and informal social gatherings
  • Extend charitable assistance to the needy and wanting
  • Promote and maintain friendship, members and other colleagues who are non members of Soyuznikis-UK
  • Promote the group locally and worldwide
Our Mission
Soyuznikis-UK is a union for Nigerians who have studied in the former Union of Soviets Socialist Republic (USSR). Soyuznikis comes from the Russian word ‘Soyuz’ meaning union. The association was founded in the summer of 2007 during the wedding ceremony of a colleague in London, the idea came about to form an umbrella organisation to bring together and embrace in friendship as it existed amongst us during our stay in the USSR was agreed.

Soyuznikis-UK is a secular and non political organisation. Membership to the group is not dependent on creed, origin, gender or sexuality. We endeavour to be a progressive organisation that will make meaningful contributions to the communities that gave us the opportunity to learn – USSR, the one that now host us - United Kingdom and most especially our nation – Nigeria. The deeds and acts of Soyuznikis-UK are guided by its constitution.

Our general meetings are held on the last Saturday of every month excluding December, when we normally hold our End of Year Party. Ideally, we as a group encourage our friends and familities to join us on our social events as a way of fostering our interpersonal relationships.

Unity Is Strength

Since inception, the association has been lead by the following persons as President. They have made efforts to foster growth and unity among members.

They are:
  1. Mr. Paul Eboh 2007 to 2009
  2. Dr. Ralph Eke 2009 to 2011
  3. Pastor Chioma Ejiofor 2011 to 2012
  4. Mr. Ebenezer Hundeyin 2012 to 2019
  5. Mr. Olushina Alaka 2019 to date


Cancel Culture - Very Divisive

The most dangerous of all falsehoods is a slightly distorted truth. The danger of instant judgements and monolithic narratives are all too prevalent in these deliberations. Where you will find cold-blooded grasping; massive sense of entitlement; an inability to show gratitude; an unrealistic expectation of puritanism from others; and a passionate performance of virtue that is well executed in the public space ( social media) but not in the intimate space of co-habitation and friendship.

These are very trying times. Technology as recent as couple of years ago was supposed to bring us all closer - remember the global village?. The emergence of an old doctrine - critical race theory the epitome of this dramatic change in attitude towards anyone with a different point of view has put paid to that paradigm. These contrive and concerted attack on one race as being the source of the biblical original sin is trivial and false period.

We insulate ourselves in ideological bubbles of similar-thinking people and refuse to countenance or even engage with the truth. We now seems to be building echo chambers with titanium and carbon fibre cladding just to make sure we do not see or hear anything different. If these cancel culture mentality is being adopted to the pandemic, may be herd immunity would have been achieved by now. We have become communities in a dislocated social fabric that is fracturing at an astonishing rate. If we do not amend this fast, rapture seems to be the only ramification.