Business

N I G E R I A

Africa In Miniature

World News in Yoruba


From The BBC

Kí ló ń fa ìdàrúdàpọ̀ lórí ìwé ìfisùn tí Nàìjíríà kọ nípa kíkópa DR Congo nínú ìdíje 2026, àti kí gan ni àjọ FIFA ń sọ nípa rẹ̀?
Ninu atẹjade FIFA, wọn ṣalaye pe awọ orilẹede mẹfa ti yoo ma koju ara wọn ninu idije FIFA inter-confederation ni Bolivia, Congo DR, Iraq, Jamaica, New Caledonia ati Suriname.


Wo àkóbá tó wà nínú àgbàdo, ẹ̀wà àti ata tí a lọ̀ ní ẹ̀rọ ìlọta fún ẹ̀dọ̀ àti kíndìnrín rẹ
Ileeṣẹ ijọba apapọ to n ṣiṣẹ iwadii (FIIRO) gbe iṣẹ iwadii kan sita pe o ṣeeṣe ki ounjẹ ti a fi ẹrọ ata ti ko mọ to lọ le ṣokunfa ki ẹdọforo, kindinrin atawọn ẹya ara miran kọṣẹ silẹ.


Ilé ẹjọ́ yọ̀ǹda Abba Kyari, wọ́n ní kò lẹ́jọ́ ọ́ jẹ́ lórí àwọn dúkìá tí kò kéde
Adajọ James Omotosho lo gbe idajọ kalẹ lori ẹsun mẹtalelogun ti ajọ to n gbe ogun ti ogun oloro lorilẹede, NDLEA fi kan Abba Kyari.


Nǹkan yan nínú ìjọ Anglican, àwọn àlùfáà tó pe ara wọn ní Gafcon lábẹ́ ìjọ náà yan bísọ́ọ̀bù àgbà tuntun tako bíṣọ́ọ̀bù Canterbury
Igun Gafcon ninu ijọ Anglican ko ara wọn jọ nílùú Abuja lati Ọjọru ọsẹ yii pẹlu èròngbà láti yan adarí ijọ Anglican ti wọn.


Ikú kẹ̀, mo kú tì, lákọ ni mo wà bí ìbọn – Ààrẹ tẹ́lẹ̀ Olusegun Obasanjo sọ̀rọ̀ lórí àwọn tó ń gbé ìròyìn ikú rẹ̀ kiri
Obasanjọ lo sọ ọrọ naa nibi eto kan ti wọn ṣe fun niluu Abeokuta lati ṣe ọjọ ibi ọdun mọkandinlaadọrun rẹ loke eepẹ.


Afurasí tó kọlu ṣọ́ọ̀ṣì ìlú Owo ṣàlàyé bí ọwọ́ DSS ṣe tẹ̀ ẹ́
Nnkan bii eeyan mọkanlelogoji ni wọn padanu ẹmi wọn ninu ikọlu naa to waye lọjọ karun un, oṣu Kẹfa, ọdun 2022, lasiko ti eeyan bii 140 ti n jọsin.


Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
Kò ṣeé má gbọ̀ọ́


Kí ló dé tí Iran fi ń ju àdó olóró sáwọn orílẹ́èdè mùsùlùmí tó wà ní àyíká rẹ̀? Ohun ti a mọ̀ rèé
Orilẹede UAE ṣalaye pe eeyan kan padanu ẹmi rẹ nigba ti awọn ologun naa gbiyanju lati da ado oloro ti Iran yin pada.


Fìtínà ni ogun tó ń wáyé láàárín Amẹ́ríkà-Israel àti Iran, ẹ yé dá sí ohun tí kò kàn yín nípa rẹ̀ – Ìgbìmọ̀ àwọn Imáàmù kìlọ̀
Awọn imaamu agba naa wa tun woye pe ohun to n ṣẹlẹ lagbaye lọwọ yii ko ṣai kan Naijiria, nitori naa adura fun ijọba lẹka gbogbo, wiwa ọna abayọ si awọn ipenija gbogbo lo yẹ ko mumu lọkan gbogbo mutumuwa.


Ọmọ bàbá onílé gún ayálégbé pa lórí èdè àyedè owó ilé
Ọkọ obinrin naa, Matthew Adeleye ati ọmọ rẹ, Tunrayo Adeleye farapa ninu iṣẹlẹ naa, ti wọn si n gba itọju lọwọ.


Iran gbìyànjú láti ṣekúpa Trump - Iléeṣẹ́ ológun US
Akọwe agba fun ileeṣẹ ologun, Pete Hagseth lo kede eyii.


Báyìí ni ogún Iran ṣe ń ṣe àkóbá fún àwọn tó fẹ́ rìn ìrìnàjò ilẹ̀ mímọ
Ogun to n lọ lọwọ ti jẹ ki ọpọ awọn alaṣẹ dena de irin-ajo oju ofurufu ni awọn apa orilẹ-ede aarin Ila-oorun, ti o si n ṣe akoba fun awọn ile-iṣẹ irin-ajo ati awọn aririn ajo Umrah.


Ipa wo ni ogun Amẹrika àti Israel sí Iran yóò ní lára Naijiiria?
Bo tilẹ jẹ pe ọpọ lo gbagbọ pe ogun yii ko kan awọn eeyan Afrika gbọngbọn, pupọ lara awọn ọmọ ilẹ Afrika to wa lawọn ilẹ ti ogun naa kan ni wọn ti n ha sọhun bayii.


Ìjoba Amẹrika kéde orúkọ àwọn ológun rẹ̀ tó ti bá ogun Iran lọ báyìí
Ọmọ ogun mẹfa lo jade laye lẹyin ti ado oloro kan ja lulẹ si ojuko ọmọ ogun Amẹrika to wa ni Port Shuaiba, lorilẹede Kuwait, lọjọ Aiku.


Èèmọ̀ ńlá ! Suleiman pa ẹ̀gbọ́n rẹ̀ nílùú Ṣẹ̀pẹ̀tẹ̀rí, Ó ní torípé ó yìnbọn fún òun lójú àlá
Nikete ti afurasi naa ṣe iṣẹ ibi ọhun tan lo na papa bora.


El Mencho: Olórí agbóògùn olóró tí wọ́n fi pósí wúrà sin òkú rẹ̀ ní Mexico
El Mencho ni o padanu ẹmi rẹ lẹyin to farapa lasiko ti ija bẹ silẹ laarín awọn oluṣọ rẹ ati awọn ikọ ologun Mexico ti wọn ran lọ lati mu un ni iparí Oṣu Keji.


Àjọ ICPC kéde àwọn nǹkan tí wọ́n kó nílé El-Rufai l'Abuja, ẹbi El-Rufai ké gbàjarè
ICPC ṣalaye pe awọn ọlọpaa tẹle awọn oṣiṣẹ ajọ naa lọ si ile El-Rufai, ati pe iyawo rẹ gan an, Hadiza El-Rufai, ati ọmọkunrin rẹ, Muhammed El-Rufai, wa nile nigba ti ajọ ICPC lọ sile rẹ.


Àwọn olùjọsìn tí wọ́n jígbé nílé Ìjọsìn Cẹ̀lẹ́ n'ilu Uso gba ìtúsílẹ̀ lẹ́yìn òbítíbitì owó.
Awọn ẹbi awọn ti wọn jigbe naa sọ di mimọ pe wọn san Millionu mẹsan naira.


Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ


Ìfìyàjẹni látọ̀dọ̀ àwọn òbí mi ni mo ka ètò ẹ̀kọ́ sí nígbà èwe mi, àmọ́ nísisìyí, mo ń k'àbámọ̀ pé mi ò kàwé – Sanyeri
Sanyeri lasiko to n sọrọ lori eto "Behind The Fame" sọ pe lasiko ti oun wa ni kekere, oun ko mọ pe fun anfani ara oun ni iwe kika jẹ, oun gbagbọ lasiko naa pe fun anfani awọn obi oun ni.


Àwa kọ́ la bẹ̀rẹ̀ ogun pẹ̀lú Iran, ṣùgbọ́n àwa la máà fòpin síi – Hegseth, alákóso ètò àbò nílẹ̀ Amẹ́ríkà
Ileeṣẹ alaabo orilẹede Israel tun sọ pe awọn ti kọlu ọkan lara awọn agba ọjẹ ẹgbẹ Hezbollah ni ilu Beirut.


Ìkọlù Amẹ́ríkà àti Israel sí Iran ti gbẹ̀mì Ayatollah Khamenei lẹ́yìn ọgbọ̀n ọdún lórí oyè; kí ni ipa rẹ̀ nínú ohun tó fa ogun náà?
Ọjọ kinni ti Amẹrika ati Israel bẹrẹ ikọli si Iran ni wọn gbẹmi Ayatollah Khamenei.


'A máa ba gbogbo àdó olóró wọn jẹ́, a máà sọ wọ́n di ẹdun arinlẹ̀' Trump ṣàlàyé ìdí tí Amẹ́ríkà àti Israel fi ń kọlu Iran
Amẹrika ati Israle kọlu Iran, amọ Iran naa ti bẹrẹ awọn akọlu si awọn orilẹede ti ọmọ ogun Israel wa.


Ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwádìí ìkú 'Obesere' olórí ọ̀dọ́ tí agbébọn jí gbé l'Ondo
Iṣẹlẹ ijinigbe bayii ti di tọrọfọnkalẹ nipinẹ Ondo, o si fẹ ẹ jọ bii pe gbogbo igba ni wọn n ji eeyan gbe nibẹ.


Àwọn agbébọn ṣekúpa àgbè, aráàlú faraya, ṣe ìfẹ̀hónúhàn ní Ondo
Awọn olugbe ogbese gbe paali pẹlu oniruru akọle si lara, bi wọn ṣe fi aidunu wọn han


PDP kò tí ì kọ́gbọ́n rárá, ẹ̀yìn Tinubu ni mo ṣì wà fún 2027-Nyesom Wike
Wike sọ eyi nigba to n ba awọn akọroyin niluu Abuja


Ìròyìn tó sọ pé alásè kan fi májèlé sínú oúnjẹ́ fún Ààrẹ Tinubu; ohun tí a mọ̀ nìyí
Yatọ si atẹjade ileeṣẹ aarẹ yii, ko tii si ileeṣẹ aarẹ kankan to tii gbe iroyin jade lori rẹ


Akire tí ìlú Ikire ní ìpínlẹ̀ Osun, Ọba Olatunde Falabi wàjà
Ọdun mọkanlelaadọrun ni ori ade naa lo loke epẹ ki ori ade.


Agbébọn padà sí agbègbè Woro ní Kwara, gbẹ̀mí èèyàn, jí oúnjẹ, fóònù, àti nǹkan míì kó lọ
Lalẹ ọjọ Abamẹta, ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu Keji yii ni iṣẹlẹ to sọ awọn araalu si siba-sibo yii waye.


Iran kéde Alireza Arafi gẹ́gẹ́ bí adelé olórí orílẹ̀ èdè lẹ́yìn ikú Ayatollah Ali Khamenei
Aarẹ Trump ni ikọlu si Iran yoo tẹsiwaju titi ti alaafia yoo fi jọba lẹkun Middle East ati ni gbogbo agbaye.


Ìjàmbá iná ṣọṣẹ́ ní òtẹ́ẹ̀lì àwọn olówò nàbì ní Ilorin, oníbàárà kan jóná mọ́lé
BBC News Yoruba kan si agbegbe ti iṣẹlẹ ijamba ina naa ti waye ti arakunrin kan to jẹ olugbe agbegbe naa ti a forukọ bo lasiri sọ pe bi ina ọba ṣe de mi ni otẹẹli naa bẹrẹ si n jo.


Ẹ wọ́gilé ìsìn ìṣọ́ òru nítorí ètò àbò tó mẹ́hẹ – Ọlọ́pàá Ondo kìlọ̀ fáráàlú
Kọmiṣọna ọlọpaa ipinlẹ ọhun, Adebowale Lawal lo fi imọran naa lede lọjọ Ẹti niluu Akure lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ lori awọn ọmọ ijọ CCC mẹfa ti awọn agbebọn ji gbe nibẹ.


Nítorí aṣọ ilé ẹ̀kọ́, bàbá akẹ́kọ̀ọ́ lọ lu olùkọ́ lálùbolẹ̀ ni Kwara
Iroyin ni niṣoju awọn akẹkọọ ni ọgbẹni Adepoju Arewa ti lu olukọ naa ni alubami ti ọpọ eeyan si n ṣe kayefi lati mọ ohun to ṣẹlẹ to to bẹẹ.


Taiwo Adegbodu, olórin ẹ̀mí ẹgbẹ́ Adegbodu Twins jáde láyé
Ekeji rẹ, Kehinde Adegbodu lo fi ikede iku Taiwo lede lonii ọjọ Isinmi.


Àjọ NSCDC kẹ́dùn ikú òṣìṣẹ́ rẹ̀ tí ọkọ̀ tẹ̀ pa l'Abuja
Agbẹnusọ ajọ naa, Babawale Afolabi sọ pe inu ajọ naa bajẹ gidigidi lori iku obinrin ọhun, ati pe iṣẹ ti bẹrẹ lati ṣeto isinku to dara fun.


Àwọn ajínigbé yìnbọn fún dẹ́rẹ́bà, jí èrò mẹ́fà gbé lọ ní Kogi
BBC News Yoruba kan si ọkan ninu awọn olugbe agbegbe ti iṣẹlẹ naa ti waye, arakunrin Olubasiri Babatunde, o si sọ ohun ti o mọ nipa rẹ.


"Tí mi ò bá rí ògùn rà fún ọmọ mi, á máa gé ara rẹ̀ jẹ títí ẹ̀jẹ̀ yóò fi máa ṣàn"
Iya ọmọ ọhun ni ọpọlọpọ ilana ibilẹ ni wọn ti gba lati tọju rẹ ki awọn dokita to ri nkan to n ṣe e gangan.


Àwọn agbébọn jí èèyàn mẹ́rin nínú ìdílé kan náà gbé ní Kwara
Isẹlẹ yii waye ni aarọ kutu ọjọ Ọjọru, ọjọ karunlelogun osu yii nibi ti wọn ti n roko.


Akọrin Fuji, Shanko Rasheed pàdánù àkọ́bí ọmọ rẹ̀, Jamal
Ní ìdájí kùtùkùtù ọjọ́ Ẹtì, ọjọ́ Kẹtàdínlọ́gbọ̀n, oṣù Kejì, ọdún 2026 ni ìṣẹ̀lẹ̀ láabi náà wáyé.


Àjọ INEC kéde ọjọ́ tuntun fún ìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Osun, ètò ìdìbò Ààrẹ 2027
Ni akọkọ, Ogunjọ oṣu Keji ọdun 2027 ni ọjọ ti INEC mu eto idibo aarẹ ati ile igbimọ aṣofin agba , ti wọn si mu ọjọ kẹfaa oṣu Kẹta gẹgẹ ọjọ fun eto idibo fun eto idibo Gomina ati ile igbimọ aṣofin ipinlẹ.


Wo ohun tó mú Busola Oke 'Eleyele' sunkún tó ń fa awuyewuye lórí ayélujára
Nínú fídíò náà, tó gba orí ayélujára ni Eleyele ti ní ṣíṣe oríire nídìí iṣẹ́ orin kíkọ kọjá níní ẹ̀bùn lásán.


Wá ojútùú sí ètò ààbò tó mẹ́hẹ kó o sì dáàbò bo ọmọ Naijiria, Alaafin àti Ooni gba Tunji Disu n'ímọ̀ràn
Ni ibẹrẹ ọsẹ yii ni Aarẹ Tinubu kede iyansipo Disu gẹgẹ bii adele ọga ọlọpaa Naijiria tuntun, lẹyin ti Kayode Egbetokun to wa ni ipo naa tẹlẹ kọwe fipo silẹ.


Ohun tí ṣíṣe àtúntò iléeṣẹ́ ọlọ̀pàá túmọ̀ sí fún Nàìjíríà
Ìpè fún ìdásílẹ̀ àwọn ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ kò ṣẹ̀yìn bí ìkọlù àwọn agbébọn àti agbéṣùmọ̀mí, jíjí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ gbé, tó fi mọ́ àwọn ìpèníjà ààbò míì ṣe ń wáyé lemọ́lemọ́ káàkiri gbogbo orílẹ̀ èdè yìí.


One Step At A Time

This old adage, more relevant than ever



Our Objective

  • Support and encourage current members as and when the need arises fairly and honestly
  • Grow our membership by reaching out through formal and informal social gatherings
  • Extend charitable assistance to the needy and wanting
  • Promote and maintain friendship, members and other colleagues who are non members of Soyuznikis-UK
  • Promote the group locally and worldwide
Our Mission
Soyuznikis-UK is a union for Nigerians who have studied in the former Union of Soviets Socialist Republic (USSR). Soyuznikis comes from the Russian word ‘Soyuz’ meaning union. The association was founded in the summer of 2007 during the wedding ceremony of a colleague in London, the idea came about to form an umbrella organisation to bring together and embrace in friendship as it existed amongst us during our stay in the USSR was agreed.

Soyuznikis-UK is a secular and non political organisation. Membership to the group is not dependent on creed, origin, gender or sexuality. We endeavour to be a progressive organisation that will make meaningful contributions to the communities that gave us the opportunity to learn – USSR, the one that now host us - United Kingdom and most especially our nation – Nigeria. The deeds and acts of Soyuznikis-UK are guided by its constitution.

Our general meetings are held on the last Saturday of every month excluding December, when we normally hold our End of Year Party. Ideally, we as a group encourage our friends and familities to join us on our social events as a way of fostering our interpersonal relationships.

Unity Is Strength

Since inception, the association has been lead by the following persons as President. They have made efforts to foster growth and unity among members.

They are:
  1. Mr. Paul Eboh 2007 to 2009
  2. Dr. Ralph Eke 2009 to 2011
  3. Pastor Chioma Ejiofor 2011 to 2012
  4. Mr. Ebenezer Hundeyin 2012 to 2019
  5. Mr. Olushina Alaka 2019 to date


Cancel Culture - Very Divisive

The most dangerous of all falsehoods is a slightly distorted truth. The danger of instant judgements and monolithic narratives are all too prevalent in these deliberations. Where you will find cold-blooded grasping; massive sense of entitlement; an inability to show gratitude; an unrealistic expectation of puritanism from others; and a passionate performance of virtue that is well executed in the public space ( social media) but not in the intimate space of co-habitation and friendship.

These are very trying times. Technology as recent as couple of years ago was supposed to bring us all closer - remember the global village?. The emergence of an old doctrine - critical race theory the epitome of this dramatic change in attitude towards anyone with a different point of view has put paid to that paradigm. These contrive and concerted attack on one race as being the source of the biblical original sin is trivial and false period.

We insulate ourselves in ideological bubbles of similar-thinking people and refuse to countenance or even engage with the truth. We now seems to be building echo chambers with titanium and carbon fibre cladding just to make sure we do not see or hear anything different. If these cancel culture mentality is being adopted to the pandemic, may be herd immunity would have been achieved by now. We have become communities in a dislocated social fabric that is fracturing at an astonishing rate. If we do not amend this fast, rapture seems to be the only ramification.